a
Es 1.1-3
.
2 Chronicles 36:22
22
a
Ní ọdún kìn-ín-ní Kirusi ọba Persia, kí ọ̀rọ̀
Olúwa
tí a tẹnu Jeremiah sọ bá à le ṣẹ pé,
Olúwa
run ẹ̀mí Kirusi ọba Persia láti ṣe ìkéde ní gbogbo ìjọba rẹ̀, ó sì kọ ọ́ sínú ìwé pẹ̀lú.
Copyright information for
YorBMYO